BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ajínigbé méjì tó ń ṣọṣẹ́ ní Kwara
Gẹgẹ bi ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ṣe kede, ọjọ Ẹti, ọjọ kọkandinlogun oṣu Kejila ọdun 2025 yii ni ọwọ ba Abubakar Usman, (Siddi) ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn (26) ati Shehu Mohammadu, (Gide) ẹni ọgbọn ọdun.
Ìwọ̀nyí làwọn orí adé àti olóṣèlú tó jáde láyé ní Naijiria àti l'Afrika lọ́dún 2025
Iwọyi lawọn eeyan jankan to jade laye ni Naijiria ati nilẹ Afrika lọdun 2025 yii.
Ìjọba àpapọ̀ sọ̀rọ̀ lórí bí yóò ṣe máa fi ọkọ̀ aráàlú tí kò dáa mọ́ pa owó wọlé ní 2026
Gẹgẹ bii ohun ti ijọba sọ, ṣiṣe eyii le pa owo ti iye rẹ to N150b lọdọdun fun oun.
Àwọn ìkọlù agbébọn àti agbéṣùmọ̀mí tó milẹ̀ tìtì lọ́dún 2025
Níṣe ni ìkọlù àwọn agbébọn àti agbéṣùmọ̀mí peléke si ní èkùn ìwọ̀ oòrùn àti ààrin gbùngbùn àríwá Nàìjíríà.
Tinubu fún Makinde ní N50bn owó ìrànwọ́ lásìkò ìbúgbàmù Bodija, èròńgbà rẹ̀ láti di ààrẹ ló ń pín PDP yẹ́lẹyẹ̀lẹ - Fayose
Ayodele Fayose sọrọ yii lori eto kan to waye nileeṣẹ tẹlifisan TVC niluu Eko.
"Kó tó di ọjọ́ Kérésì la ti fẹ́ yín àdó olóró mọ́ àwọn agbébọn, síbẹ̀, Amẹrika ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mú ẹyẹ bọ̀ lápò"
Ìkéde yìí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan tí Akọwe ileeṣẹ ologun fún Amẹrika, Pete Hegseth, fi sójú òpó ayélujára rẹ̀.
Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà àti olórin tó kú ní 2025
Kanran, Asakoko, Sanku àti ọ̀pọ̀ amúlùdùn míràn wà lára àwọn amúlùdùn tí BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ wọn nínú àwọn ènìyàn tó bá 2025 lọ.
Kí ló ń jẹ́ Eyo, níbo ló ti wá sílú Eko, àwọn wo ló ń gbé e, kí sì ni èèwọ̀ rẹ̀?
Bí àṣekágbá ọdún Eyo ṣe ń wáyé lónìí, BBC News Yorùbá ṣe ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn nípa ohun tí ọdún Eyo dá lé lórí.
Ayédèrú òṣìṣẹ́ aṣọ́bodè lu Soun Ogbomoso ní jìbìtì N39.5m, ọ̀rọ̀ di tilé ẹjọ́
Muhammed, ẹni ọdun marundinlaadọta (45) pe ara rẹ ni ọga aṣọbode ipinlẹ Oyo fun Kabiyesi Olaoye Ghandi láti gba owó tuulu lọ́wọ́ rẹ̀.
Táńkà epo gbiná lọ́jọ́ Kérésì, èèyàn méji kú ní márosẹ̀ Eko sí Badagry
'Lagos State Traffic Management Authority' (LASTMA) to n ri si igbokegbodo ọkọ niluu Eko, fidi ijamba naa mulẹ.
Boxing Day: Kí ni ìdí tí wọ́n fi ń pe ọjọ́ kejì ọdún Kérésì ní Boxing Day?
Boxing Day ko ni nnkankan ṣe pẹlu ẹṣẹ kíkàn gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe lero.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ọlọ́pàá tó tẹ̀lé Akpabio wá síbi oyè Seyi Tinubu àti Yari ko àgbákò ikú òjijì bí ọkọ̀ agbepo ṣe tẹ̀ ẹ́ lórí mọ́lẹ̀ n'Ibadan
Ààrẹ ilé aṣòfin àgbà fúnra rẹ lo kéde ìṣẹ̀lẹ̀ yìí níbi ìjókòó ilé aṣòfin àpapọ̀ to wáyé lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ana.
Ọba alayé tí wọ́n jí gbé ní Kwara gba ìtúsílẹ̀
Agbẹnusọ ilu naa, Ayinla Lawal, fidi ẹ mulẹ pe Ọba Kamilu Salami ti kuro ni akata ajinigbe.
Àjẹ́ Kérésì, kíkó ìgbálẹ̀ pamọ́, àti àwọ̀n àṣà mìí tí o kò gbọ́ rí nípa Kérésìmesì
Lónìí àyájọ́ ọjọ́ Kérésì, BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn àṣà àti ìṣe tó yàtọ̀ sí ti gbogbo ènìyàn lásìkò ọdún tó ń wáyé làwọn àgbègbè kan ní àgbáyé.
Mo kábàámọ̀ pé mo ṣe àtìlẹyìn fún Tinubu ní 2023, èmi gan ní ohun tó yẹ láti di ààrẹ Nàìjíríà - Seyi Makinde
Ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun, ọjọ́ Kẹtàlélógún, oṣù Kejìlá ni Makinde sọ̀rọ̀ níbi àpérò tó ṣe pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn nílé ìjọba tó wà ní Agodi, Ibadan, ìpínlẹ̀ Oyo.
Èèyàn 5 kú, 35 farapa yánna-yànna lásìkò ìṣẹ̀lẹ̀ àdó olóró tó bú ní Mọ́ṣáláṣí ní Maiduguri - Ọlọ́pàá
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wáyé lásìkò tí àdó olóró ṣàdédé bù nínú Mọsalasi náà, tó sì pa agbésùnmọ̀mí to yín ado ikú náà àti ọ̀pọ̀ èèyàn.
Àwọn ẹ̀bùn mẹ́wàá tí o lè fún àwọn èèyàn lásìkò Kérésìmesì láì pa àpò rẹ lára
BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ awọn ẹbun mẹwaa ti owo wọn ko pọju ti o le ra fun awọn eeyan rẹ lasiko pọpọṣinṣin ọdun Keresimesi yii.
Ìjàmbá iná jó ilé ìtajà lọ́jà Balogun l'Eko lọ́dún Kérésì ku ọ̀la, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣófò
Àtẹ̀jáde tí àjọ tó ń mójútó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko ìyẹn Lagos State Emergency Management Agency, LASEMA ṣe sọ, wọ́n ní àjà kẹrin ni iná náà ti dédé ṣẹ́yọ.
Wo awọn ìjọ ẹlẹ́sìn ìgbàgbọ́ tí kì í ṣe ọdún Kérésìmesì
Gẹgẹ bi igbagbọ awọn ẹlẹsin Kristi, ọdun Keresimesi n ṣami ìbí Jesu olugbala ni, ẹni ti a gbọ pe wọn bi si ibujẹ ẹran ni ilu Bethlehem, ti ìbí rẹ si yatọ, to jẹ mimọ lati ode ọrun.
Àlàyé rèé lórí bí nọ́mbà NIN àti ìwé ẹ̀rí CAC ṣe le rọ́pò nọmbà owó orí rẹ lọ́dún tuntun
FIRS ni awọn ti kii pa owo wọle bii awọn akẹkọọ atawọn ti wọn ṣi wa labẹ obi tabi alagbatọ wọn ko nilo Tax ID kankan.
Kéré ó! Májèlé tó léwu fún àgọ́ ara ni oúnjẹ 'Indomie Vegetable Flavour', a ti ń kó o kúrò lọ́jà – NAFDAC kìlọ̀
Ọ̀gá agba ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisola Adeyeye Indomie ọhun ko wa lode fun tita ni Naijiria lásìkò yii nitori orilẹede France ni wọn ti n pese rẹ.
Wasiu Ayinde kéde pé òun kò du ipò Awujalẹ mọ́ lẹ́yìn tó lulẹ̀ lórí ẹjọ tó pé tako ìgbésẹ̀ yíyan Awujale tuntun
Adajọ A. A. Omoniyi da ẹjọ́ Wasiu Ayinde nù lórí àwíjàre pé ẹjọ́ náà k o lẹsẹ nilẹ ati pe ko si ẹri to dantọ lati gbe ẹbẹ naa lẹyin.
Ìtàn rèé nípa bí ikú Bola Ige ṣe ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọdún 24 tó jáde láyé, láì mú ẹni tó pa á
Bó ṣe pé ọdún mẹ́rìnlélógún tí àgbà Amòfin Bola Ige jáde láyé, BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ ìtàn àwọn agbébọn ṣe pa á àti kókó ohun tó gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn, èsì, iye góòlù àti ipò tí ikọ̀ agbábọ́ọ́lù kọ̀ọ̀kan wà nínú ìdíje Afcon 2025
BBC News Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn, èsì, iye góòlù àti ipò tí ikọ̀ agbábọ́ọ́lù kọ̀ọ̀kan wà nínú ìdíje Afcon 2025.
Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ báwọn ọmọ bíbí Ogbomoso nile àti lókè òkun ṣe péjú fún àjọ̀dún àṣà ìlú wọn
BBC News Yorùbá péjú síbi ayẹyẹ agbelarugẹ àṣà nilu Ogbomoso, àkójọpọ̀ ìròyìn rèé nípa ohun tó wáyé níbẹ̀
Ohun tó wáyé tẹ́lẹ̀ ti lọ, ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Tanzania ni mò gbájúmọ́ báyìí – Eric Chelle, Akọ́nimọọ̀ọ́gbá Super Eagles
Chelle tun wọgile ọrọ kan to n lọ kiri pe aseyọri ninu idije ni yoo sọ boya yoo tẹsiwaju gẹgẹ bii Akọnimọọgba Super Eagles.
"Ìtẹ́ Aláàfin ló máa ń pàṣẹ fún gbogbo ilẹ̀ Yorùbá, torí náà, èmi nìkan lọba alayé tó lè fi èèyàn jẹ oyè fún ilẹ̀ Yorùbá"
Nibi ayẹyẹ naa ni ilu Oyo ti gba alejo awọn ọtọkulu, awọn oloselu ati awọn lọbalọba lati origun mẹrin gbogbo ilẹ Yoruba.
Kí ló dé tí ìjọba Amẹ́ríkà pàṣẹ fún 'Ambassador' rẹ̀ ní Nàìjíríà láti padà sílé?
Ìròyìn náà ni ó lè ní orílẹ̀èdè bíi mẹ́rìnlélógún tí isiporọpo náà kan àmọ́ ọ̀pọ̀ wọn lo wa nílẹ̀ Áfríkà.
Àlàyé rèé lórí ìdí tí o ṣe gbọdọ̀ ṣàyẹ̀wò mímu oògùn olóró, tí o bá fẹ́ gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀
Atẹjade kan lati ọọfisi akọwe agba si ijọba apapọ, Segun Imohiosen lọ kéde bẹẹ.
Sunday Igboho fọnmú bí afurasí Fúlàní ṣe ṣá àgbẹ̀ mẹ́ta pa nílùú rẹ̀, fi ewé ìkìlọ̀ mọ́ ìjọba létí
Igboho ke gbajare si ijọba apapọ lori iṣẹlẹ naa, pẹlu alaye pe suuru awọn eeyan oun ti fẹ dopin.
Agbálẹ̀ ojú pópó pàdé ikú òjijì lópin ọdún lásìkò tí Dáńfó tó ń rìfáàsì lójú ọ̀nà márosẹ̀ kọlù ú
Ajọ tó ń ṣàkóso eto irinna lójú popo nipinlẹ Eko, LASTMA, tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà soju rẹ, salaye bí ọ̀rọ̀ náà ṣe jẹ́ àtẹ̀jáde kan tó fisita loju opo ayelujara X rẹ.
Àwọn ajínigbé bínú tán, kọ̀ láti gba owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ ẹbí ní Kwara
Tẹ o ba gbagbe, ọjọ kẹrinlelogun osu Kọkanla ọdun 2025 ni awọn agbebọn ya wọ ilu Isapa, nijọba ibilẹ Ekiti, ti wọn si gbe awọn araalu mẹwaa lọ lẹyin ti wọn ti rọjo ibọn kalẹ








































































